23,99 €
inkl. MwSt.

Versandfertig in über 4 Wochen
  • Broschiertes Buch

Èyí ni àw¿n EWÌ À¿EY¿RÍ ÒMÌNIRA NÀÍJÍRÍÀ tí mo kó j¿ pap¿¿: Ó j¿¿ ohùn ìdùnnú fún mí púp¿¿ láti k¿ ìwé àkój¿p¿¿ ewì yìí. A k¿ ìwé ewì yìí ni àsìkò tí oríl¿¿-èdè Nàíjíríà pé ¿g¿¿ta ¿dún láti ¿e àyàjó¿ ¿j¿¿ ìbí r¿¿ náà; ti wón ¿e À¿EY¿RÍ ÒMÌNIRA ¿G¿TA ¿DÚN ORÍL¿¿ ÈDÈ NÀÍJÍRÍÀ náà. Àw¿n ewì j¿ ohun àbálàye tí ó j¿ ¿m¿ Yorùbá lógún. Ní ayé àtij¿¿ ní ilè Yorùbá, ò un ni àw¿n bàbá-¿lá wa máa ¿ lò fún ìmò¿, ìmò¿ràn àti ¿¿k¿¿, ¿ùgbó¿n won kìí k¿¿¿ síl¿¿ nítorí pé, w¿n kò ní ìmò¿ mò¿ó¿k¿¿mò¿ó¿kà rárá. Orísírísí ewì ni ó wa, orísírísí ¿¿nà ni a sì lè pín ewì sí. Èrò ¿kàn mí ní pé a ó gbàdùn ìwé àkój¿p¿¿…mehr

Produktbeschreibung
Èyí ni àw¿n EWÌ À¿EY¿RÍ ÒMÌNIRA NÀÍJÍRÍÀ tí mo kó j¿ pap¿¿: Ó j¿¿ ohùn ìdùnnú fún mí púp¿¿ láti k¿ ìwé àkój¿p¿¿ ewì yìí. A k¿ ìwé ewì yìí ni àsìkò tí oríl¿¿-èdè Nàíjíríà pé ¿g¿¿ta ¿dún láti ¿e àyàjó¿ ¿j¿¿ ìbí r¿¿ náà; ti wón ¿e À¿EY¿RÍ ÒMÌNIRA ¿G¿TA ¿DÚN ORÍL¿¿ ÈDÈ NÀÍJÍRÍÀ náà. Àw¿n ewì j¿ ohun àbálàye tí ó j¿ ¿m¿ Yorùbá lógún. Ní ayé àtij¿¿ ní ilè Yorùbá, ò un ni àw¿n bàbá-¿lá wa máa ¿ lò fún ìmò¿, ìmò¿ràn àti ¿¿k¿¿, ¿ùgbó¿n won kìí k¿¿¿ síl¿¿ nítorí pé, w¿n kò ní ìmò¿ mò¿ó¿k¿¿mò¿ó¿kà rárá. Orísírísí ewì ni ó wa, orísírísí ¿¿nà ni a sì lè pín ewì sí. Èrò ¿kàn mí ní pé a ó gbàdùn ìwé àkój¿p¿¿ ewì yìí. Nàìjíríà (/nä¿d¿¿r¿¿/) j¿¿ Oríl¿¿-èdè Olómìnira. Ìj¿ba Àpap¿¿ il¿¿ Nàìjíríà j¿¿ oríl¿¿-èdè tí ó ní ìj¿ba ìpínl¿¿ m¿¿rindínlógójì tó fi m¿¿ Agb¿¿gb¿¿ Olúìlú Ìj¿ba Àpap¿¿. Oríl¿¿-èdè Nàìjíríà wà ní apá Iw¿¿ Oòrùn il¿¿ Áfríkà. Oríl¿¿-èdè yí pààlà p¿¿lú oríl¿¿-èdè Benin ní apá ìw¿¿ Oòrùn, ó tún pààlà p¿¿lú oríl¿¿-èdè olómìnira ti Nij¿r ní apá àríwá, Chad àti Kam¿róòn ní apá ìlà Oòrùn àti Òkun Atlantiki ni apá gúúsù. Abuja ni ó j¿¿ Olú-Ìlú fún oríl¿¿-èdè náà. Bí ó til¿¿ j¿¿ pé Nàìjíríà ní ¿¿yà púp¿¿, àw¿n ¿¿yà m¿¿ta ni w¿¿n tóbi jùl¿. Àw¿n w¿¿nyí ni ¿¿yà Yorùbá, ¿¿ya Ìgbò ati ¿¿yà Hausa.
Autorenporträt
Mercy Olufunmilayo Adesanya-Davies BA (Ife), MA English (Ilorin), PhD Applied Linguistics and Communication Studies (Port Harcourt) and PGDE est une linguiste, une poétesse, une militante de l'éducation et une experte dans le domaine des études de communication. Également évêque, elle est titulaire d'un doctorat honorifique en théologie (DD) de la Northwestern Christian University, aux États-Unis.